it is not about getting permission from the king to travel on pilgrimage but just a curtsey of honour to inform the king. King is the leader under right and leader of the whole community but chief imam is just a religion leader.
Hum dont say that, you don't know why he didn't tell the king you're two judgemental you can't say that because of the king is not a Muslim, please that's not a good talk okay
Baba kan bayi tí a npe ni Baba Jẹ̀lili, Musulumi ni wọ́n ni àdúgbò wá ní Isalẹ̀-Aké, ní Abẹ́òkúta. Tailor ni bàbá yẹn ọ̀dọ̀ wọn la sì má ngbé aṣọ school àti èyí tí àwọn bàbà wa máa nwọ̀ lọ fún ríran ..Nígbàtí baba Jẹ̀lili nlọ si Hajj wọ́n wá sí ilé wa ni Ìbarà láti wá wí fún bàbá àti màmá wa wípé àwọn nlọ si Mecca fún Hajj. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé Christian ni wá.. Àwọn bàbá àti màmá sì ṣe àdúrà fún bàbá Jẹ̀lili.. Mí ò wá rántí bóyá wọ́n fún bàbá yẹn l'owo o. Baba Jẹ́lili travel wá láti Ìsàlẹ̀-Aké wá dagbere Mecca fún àwọn parents mi. Mo rántí dáadáa.. Christian ni wá tí bàbá wa jẹ́ Ọ̀gá Akọrin ni Catholic Church nígbà náà. Baba Jẹ̀lili ni wọ́n má nran aṣọ school fún wa ní kékeré. A ti kúrò ní ilé mai rent sí ilé tiwa gangan tí bàbá wa kọ́ nígbà náà. Baba Jẹ̀lili tí salaisi ni bí 1990s yẹn, bàbá wa náà tí kú ní 1998.. Mama nìkan ló kù mo sì mọ̀ pé àwọn náà ṣì rántí dáadáa. Èyí ni lati fi kín ọ̀rọ̀ yín lẹ̀yìn.. Ko ni nkan ṣe pẹ̀lú ẹ̀sìn.. Àṣà ni..
I have said it severely, this mufuti is the evil one behind all the crisis on imaamship in Ogbomoso. He is most likely the one who imported the so-called imaam and wants to install him by force. He just looked for a fanatics like him to create a crisis that will open the door for their evil agenda. The chosen christian king will most likely frustrate their agenda. So the battle was to frustrate or remove him from the way. Their mission is to forcefully claim Ogbomoso for the Fulanis through Islam as sponsored by Saudi and the northern Emirates just like Oluwo is doing in Iwo.They want to claim all Yoruba land for Alimi with the sword through the guise of Islam, like they did in Ilorin. It is jihadist and terrorist agenda. Imagine someone living in Ogbomoso land saying he and the Muslims are not under the authority of the king. He is openly instigating and mobilizing the muslims to riot against the king.Thank God, Ogbomoso muslims are not fools or heartless beasts.This man and his imported imaam have done more than enough to be unrobed and put behind bars.Thanks to you Aare Laji Abass and the League of imaam of Ogbomoso land for being fair and just. Islamic terrorism under any guise must not be allowed in any part of Yorubaland. The royal stool of Ogbomoso and any Yorubaland is open for qualified, suitable and matured candidate from any of the religions, but not for traitors, fanatics, thugs and terrorists. Long live Oba Ghandi the Soun of Ogbomoso. Peace upon Ogbomoso land and people.
@@kazeemabdulsalam-j1m Àwọn ọlọ́pọlọ pípé mọ̀ wípé ó fi í ìkan jọ ara wọn. Àti àwọn tí wọ́n bá gbọ́ àpèjúwe pẹ̀lú làákàyè tí Ààrẹ Òpìtàn fi gbé ọ̀rọ̀ na kalẹ̀..
That mufti ìwo should be taken serious, the man is not Yoruba and he had not hide his word and intention to handle over ìwo and many other Yoruba cities to Fulani caliphate it's never about Islam but ethnic cleansing
Muslims dont want to respect our traditions but when they travel south they respect emir and bow, because they are superior to your own king ? Can any Christian leader talk to the emir of iwo like that ? Forgetting your origin because of religion ? So because hes a Christian the imam can travel without permission and telling the king? If anything should happen while the imam is jot around who will take responsible if not the king.
Oloriburuku ni awon eleyi ,agbabode ni won,bi mufti se nfi owo lale ni iwo ni yunusa naa fe maa fi owo lale ni Ogbomosho Ogbomosho ni awon dindinrin yi so di yepere bee yen Ti ayilara family ba fe tun ero won pa lori yunusa tele nitori mufti yi ko ye ki won gba fun un Nitoripe elewu eniyan ni mufti eyan meji ko si le jo rinpo biko se pe won re Kini ase ti Ilu Iwo ni lori Ogbomosho Kini won si gbojule ti won fi nri oba yi fin bi pe awon ni won nbo oba yi Tani mufti legbe oba Gandy,oba Gandy to yunusa bi lomo kilo de ti awon eyan winyi ko ni ibowo fun agba,kilo pa Ogbomosho ati Ilu iwo po Dajudaju awon omo leyin yunusa ti nsepade pelu mufti lori oba Gandy ni ilu iwo Nitoripe awon oro kab iti ti mufti iwo nso wonyi o ju enu re lo Eyin christian ema wo oba yi niran ekuku mo pe ohun ija wa kii se ibon kii se ada kii si se oko E fi adura ran oba yi lowo Inumi dun pe a o gbo ibi kan ti oba yi ti soro buburu bi won ti nwe nu si to Olorun a gba ija won ja
Gbogbo oro ti Aare opitan so ninu fonran yii mu ori pipe wa. Oluko agba to tun je Onibode ile Yoruba jewo nibiyi wipe imo lo ni adini, ogbon ko gbe rara.
Most of the commenting did not know the protocol and procedures in Iwo. All of you should obtain a copy of the letter of appointment of installation of the Imam of Central mosque in Ogbomoso, which Imam Taliat signed before he became an Imam and read it. What is obtained in one community may not be the norm in another. That's the area most of you did not look at closely before dabling into matter that you did not have knowledge about.
Mufti Taun Iwo Town your knowledge is too shallow about Islam in Yoruba land. In Ikenne town in Ogun State Central Mosque was shut down for many years on the order of Late Chief Mrs H.I.D.Awolowo. This man is a very STUPID AND NON CULTURED.
@@james_smith9 Talk to your brother not to overstep his boundary because he would soon regret it sooner or later. Omo eru ati alejo ni Mufti taun igbira ni ilu iwo je.
This is not a matter of nigerian or human beings. A visitor in a town is a visitor, so there are some post that will l not be given To a visitor @adeyinkabolaji
You're a TRUTH-SAYER! May the Almighty :God continue to bless your home, bless your programme and bless Ibadan Land bcos of you🙏 Continue your good-work The ALMIGHTY GOD is behind you..🤔
Baba don't be hypocrites for Islam, Soun Ogbomosho show it that he hated Chief of Imam Ogbomosho, that is why chief Imam distance his from Baba Soun Ogbomosho. Those people hate Islam they wanted to kill progress 💪 of Islam in Yoruba land . Once again don't be hypocrite to Islam.
There is no different from this iwo mufti and oluwo in character and in speech,very shameful, they both lack home training and good culture,that is why they refer to them as "omo ale yoruba" oba kan ole pase fun muslim ,sugbon goverment can stop muslim from going to mecca during covid 19. What a confusion Awon eru esin.
It's a pity a lot of people talk out of knowledge while some talk wirh half knowlegde. If Baa Pitan is saying whar suits u does not mean he's abosulutely correct. He talked about Yoruba Obas appointing Imams and having power to remove them except Ibadan, its a blatant lie from the pit of hell. Abeokuta Central mosque named Kobiti, is far from Aafin Alake. Infact, all mosques in Abeokuta are very far from any of the palaces. I have said it before and I'll say it again, no Oba appoints or can remove an Imam in Abeokuta. My father was an Imam, and the then Gov Daniel threatens to remove him and send d message through Olowu of Owu ، Oba Dosunmi, and my father told him he dares not cos neither the Oba nor the Gov has d power. Coming to d issue at hand, I so much respect the traditional institution but u have to ask urself a critical question that what is in Ogbomosho tradition can stand in the face of law? Do u think an Oba cannot do what is against the law? Yes, he can. The fact that Oba appoint Imam in Ogbomossho doesnt nean it's right. Islam has a its rules and an Imam is never a traditional title in a place that thrives on culture ans tradition. An Oba will have that power in in place that thrives on Islamic tradition and culture. So not forget, constitution guarantees free movement free choice of religion. If the query goes to court, it is a nullity. Informing anyone of ur pilgrimage is a priviledge not a right even if u sign a document that cannot stand before the law, it's only valid dor as long as it is not contested before the law. Can anyone remember that Mikel Obi signed for Man u before he signed for Chelsea but the court nulified Man u contract.
You're putting petrol inside fire, you're not helping matters at all. Baapitan are you telling us stories about the fight in Ogbomóshó or what is today's program about?
That's why America is great. It's built on ideas not religion, tribes or tradition. Nigeria, we are failing because we put our tribes, religion and tradition before the Nation.
Am sure that Mufutau iwo will soon put tolia of ogbomosho into trouble. Tolia will soon be removed. He is not a true son of Ayilara, he has bad blood of b.strd in him fighting Oba Ghandi, omo oko ki huwa bi omo ale! Ikun nde dede, dede nde ‘kun loro imam tolia!
Baba onpitan ,I so much love you ,nitiripe Olorun fun yin ni ogbon ,oye ati imon ,eyinki Se adaluru ,atun ilu se ni eyin ,Mogbadura wipe eti goke eni jabo lailai,ese eku atunse
Imamum Ogbomoso is doing what he is doing because Oba ogbomoso is not a Muslim and there is no Law that said the king of a land in Yoruba lands must be a Muslim.
Baba wa, emi yin a gun. Eo nii ri ohun gbe sonu bi ko se ibi omo. Oro yin o ma nii daru, Sir. Thank you for being factual and sincere. Oro naa tile mba ni ninu je gegebi omo Yoruba. Haba, ki la fee fi sile de awon omo gan? Atunse ati atunto gbodo wa ni ilu Ogbomosho oh. Ire oh!
nnkan mase iran yoruba bayi oo, ipo oba ko wa ni ola, aponle mon. ko wa si aponle mon. oba lo ni ilu, olori ilu, awon alfa, pastor are messanger and servant they are subject to king
Ilu tabi Ile ti o ba n toro, omo ale ibe ni ko ti dagba. Se awon eniyan yi le ri Emir Ilorin, Kano, abi oba Saudi fin bi ti Taolat ati Mufti yi? O ma se o.... Sebi won so pe esin alaafia ni Musulimi ni? Alaafia naa wa da. Awon oyinbo amunisin ni won da gbogbo re sile to won so oba ilu di yepere.
May God bless you sir. You’re right with everything you just said but don’t forget Soun was the one that make this man ridiculed him like that. He went to knee down b4 pastor for prayer so how did you expect his subjects to respect him when he didn’t respect himself and the high rank sit he is sitting on. A whole SOUN. Soun is not a small king in Yoruba land.
You don't even need to go far. E maa lo jina, mufti Iwo ko kere, ko si lo si irin ajo Nigbati aawo fi be sile laarin Oluwo ati chief imam agba of iwo, ti Oluwo fi le chief imam kuro ni central mosque of iwo.Ti o si fee yo kuro ni chief Imam.
EYIN ALUFA ODE ONI E MO BA ILU JE,A BE OBA NI IMAM ILU WA.EYIN ALUFA ODE ONI ORO YIN FE SU AWON ENIYAN, E KOJU MO OUN TI ALLAH GBE LE YIN LOWO,E BEERU ELEDA, EDUMARE, ALLAH.
Baba wa Opitan,Olorun yio ma wa pelu yin. Imam Ogbomosho Yi ti fi ara re han pe omo Ale lohun nitooto. Omode to ba Fe dagba ko ni yaju si Agbalagba, shee oye esin ju oye Oba lo ni? Imam Ogbomosho ati Imam Iwo ko ni pe subu lagbara Olorun ati awon onile.
Chief opitan soo kinni yen fun won ko yen daada. Olorun oni gba fun won ki won da ile yoruba ruu.awa oni ibo miran ti anloo.omo yoruba niwa. E jee ko yee Won daradara.
Any true born yoruba will not open his mouth to be insulting Oba. They should do proper check on the historical background of Dauda Molaasan to know from where his forefathers migrated from before they settled down in Iwo.
Mufti ki i se Yorùbá, nitori gbogbo oro re ko ya to si ti afofun gbe mu, ki a si mo gba gbe pe Oloselu onijibiti ni mufti odaran yi, bi ki ile Yorùbá da ru ni oma hun se, ki gbogbo agba gba ni ile Yorùbá mo bi won yo se fi mufti jo fin, nitori bi won se bere ni ilorin ni eleyi, oba 419, to hun fi esin Bo ju se ise aburu.
Onpitan are you from this world.Can't hear that Soun have banned Chief imam from the palace and he was not to enter or interfere to palace activities since February 2024.
It's very unfortunate in Yorubaland that our people are bringing sentiments to many things. The same organisation wrote a letter of threat to my school to charge my school to court because of one of our students who comes from Iwo. By the end, the so-called boy eventually turns to become our friend.
Honestly, I always like your program because you are always speaking the truth without any restrictions. . God bless you sir. Ogbon, lakaye ati oye ti Olorun fun yin ko ni dibaje ni oruko Jesu. E ku agba sir. Inu mi dun fun otito ati ododo ti e n so lori oro yi. Olorun yo ma wa pelu yin o. Opolopo awon eniyan ni won mo otito sugbon won ko lati so ododo. Won n gbe lehin ibaje nitori owo.
Awọn bàbà wá ti sọ wípé "Ilu tí ó bá ń toro, awọn ọmọ aale ilé na kò ti dàgbà". "Ìlú tí kò sì òfin, ìjìyà kò sì ní nibẹ". Whoever mock his origin in mud, his origin will rub him in pit. Agba yin a dalẹ olùkọ́ agba Ààrẹ Laji Abass ❤