Let the (Kings) Awon Oba put Ifa oracle down and ask what to do about Yoruba nation. Yoruba nation is the answer. They should not listen or bow for the Federal Republic of division.Mama Asake may God Almighty guide you and protect you and your entire family in Jesus Christ name.we love your program. God bless your heart. (AMEN)
It's advisable that our obas respect the wishes of their subjects by sticking to what they want. If they work against the self determination of our Yoruba Nation, they stand the chance of regreting it.
Oonirisa loye kole ipade toripe oun ni olori awon Oba ile Yoruba emi gba awon Oba niyanju pe ki won mase jeki ipade na waye ni Odo oba elegusin tori onibode no ko see finu tan ore Fulani ni oo Sunday lgboho ko gbodo lo si ipade yen
huunmm inu agbole lati npari ija omo ile . inu Aafin ufe lo ye ki iru ipade yi ti waye . nitoripe nibe ni gbogbo ori Ade ti jade .BAB WA Ooni ibi gereje la nba Agba .
Gbogbo Eyin lọba l'ọba ilẹ yoruba, hàáà se bí awọn baba nla yín se lo igba níyì. Oga o, ẹti wa nfi ori adé wọ gbagede. Bàbá wa Ọọni Ile ifẹ olórí aládé gbogbo, Arole Oodua. Ìpàdé lọba l'ọba ilẹ yoruba hmmmm, ilẹ Oodua di ọwọ yin o. Baba wa arole Oodua, ẹse re kodara gbogbo ọmọ Yorùbá n'wo yin o. Eyiti wọn pawa ti to gẹ o.
Nipa ti ipade ti Tinubu fe ba awon oba ile Yoruba se, Tinubu kole pe awon Oba si ipade ti oma so esp rere fun Yoruba Nation, bikose fun atako fun Yoruba Nation, Pelu imo ti ara re nikan
Fun gbogbo oba alade, ko tonaa fun awon oba yin fun ipade ti yio wa ye ni 7/11/2024. Nitori ile ife ni gbogbo yoruba ti se wa. Pls ojaja ooni tiwa, ile ife ni o ye fun ipade yi. Nitori oto ni ade isebaye otoni ade government, Ase be ni ile ife, gbogbo osa be ni ile ife. Ooni osa ema bawon lowo ninu awon odale. E mase ta Ase ile yoruba. Odua agbe wa.
Baba to soro lori oduduwa ko ye Kan so be,se awon wa laye nigba oduduwa ni,ati wipe ki won wa so ibi ti oduduwa ku si fun wa.niwongba ti won o ba le so ,kay ye pa itan ti won ma fi ma bu awa omo o tu a jire,asiko itan lori awon babanla wa ko niyi o Ire o.
E jeki a fi awon oba wonyi sile pelu iwa won. Lati ojo ti baba professor Banji Akintoye and chief Sunday Igboho pelu eyin Yoruba bloggers ati ajijagbara ti nsoro nipa OMINIRA YORUBA, awon oba melo ni o se atilehin fun yin. Nkan ti won ma je ko jeki won gbon. Nkan ti mo fe ki e mo ni wipe, millions awon oba kan ko le da ise Olorun lori Yoruba Nation duro rara. E tesiwaju ninu akitiyan yin lori oro Yoruba Nation, Olorun ko ni pada lehin yin titi eyin yio fi se aseyori.
Mama mi Asake, e ku ise takuntakun ti e nse yii o. I’m so sorry to disagree with the man that spoke so much as if he was there when Oduduwa lived. Awolowo committed suicide? Jakande revealed the plans? Now, can we ask this wise and knowledgeable man what has he done for the Yoruba people? About the killings, that it was the Hausa that were killing the people? Can he show any evidence? Can he show us one Hausa emir? How many Hausas are governors? Sir, we are not blind, we can distinguish the Fulanis from the Hausas. What solutions are you bringing to the table?